Ìnira lábẹ́ Ìjọba Tinúubú kọjá Sísọ - Emir ìlú Kánò sọ fún aya Ààrẹ Tinúubú
Home - News

Ìnira lábẹ́ Ìjọba Tinúubú kọjá Sísọ - Emir ìlú Kánò sọ fún aya Ààrẹ Tinúubú

Feb. 13, 2024

Ìnira lábẹ́ Ìjọba Tinúubú kọjá Sísọ - Emir ìlú Kánò sọ fún aya Ààrẹ Tinúubú

Admin By Adewale Adewale
  • 246
  • 42 min
  • 0

Emir Ìpínl̀ Kánò, Àlàáji Àmínù Adó Báyéró ĺj́ Ajé s fún obìnrin àḱḱ, ìyn aya Ààr oríl̀-èdè Nàìjíríà, arábìnrin Olúr̀mí Tinúubú nígbà tí ó wá e àb̀wò sí ní ààfin r̀ kí ó bá Ààr B́lá Ahmed Tinúubú s̀r̀ lórí ìpèníjà tó ń bá àwon omo ilé yi fínra.

Nígbà tí ó ń gba aya oríl̀ èdè Nàìjíríà lálejò, ó ní, “bí ó til̀ j́ pé a ní ̀nà oríiríi láti fi èròńgbà wa hàn àḿ ti aya Ààr yóò tètè dé ̀d̀ Ààr ju ̀nà yòókù l."

Èdè Haúsá ni ó fi s r yìí àḿ ̀kan lára àwn agbèf́bà ló e ògbif̀ r̀ sí èdè G̀́sì.

Ó s pé, “Mo gbà pé àjogúnbá ni wàhálà il̀ yìí àḿ èyí tó burú jáì ni ti ìgbé ayé tí kò fara r lásìkò ìjba tó wà lóde báyìí èyí tí ó ń f́ ̀nà àbáy ní kíákíá”.

Bákan náà, Emir tún ḿnubà èròńgbà láti gbé àwn ̀ka iléeṣẹ́ ìjba kan kúrò ní olú-ìlú il̀ wa ní Àbújá l sí Ìpínl̀ Ààr.

Àmínù Adó Báyéró s pé, ara ń fu òun bí Ààr e ń gbèrò láti gbé ̀ka kan tó j́ gbòógì ní ilé ìfowópaḿ àpap̀ àti àj tó ń àkóso k̀ ofurufu l sí ìpínl̀ Èkó.

Nínú ̀r̀ r̀, Emir ti ìlú Kánò s pé, "òun ti ń gba oríiríi àt̀jíṣẹ́ lórí ̀r̀ tó ń jà rànyìn láti ̀d̀ àwn aráàlú tí ̀g̀̀r̀ wn sì ń kminú ìgbés̀ Ààr yìí.

Ó gba ìjba àpap̀ lám̀ràn láti má e figbá-kan-b̀kan nínú fún m Nàìjíríà lórí ̀r̀ yìí kí ẃn sì bá wn s èdè tí ẃn gb́”.

Bákan náà, Báyéró r Ààr láti túb̀ máa la àwn aráàlú ĺỳ lórí ̀r̀ yìí, ó ní, “òun ǵǵ bí nìkan kò lè s èròńgbà ìjba pàtó, ó y kí ó làá hàn gbogbo m Nàìjíríà èrèdí tí wn e ń f́ dá àwn ̀ka ilé ìfowópaḿ àpap̀ àti ti k ofurufu padà sí ìpínl̀ Èkó.

"Ètò ààbò tó ḿh náà jẹ́ ìpèníjà àti wàhálà tó ń bá àwn èèyàn ẁyá ìjà, mo sì m̀ pé ìjba tó wà lóde báyìí náà bá a b́̀ ni àḿ a gb́d̀ gbé ìgbés̀ akin kí ìpèníjà yìí lè rodò l mumi”.

Ó lu aya Ààr ĺg nu bí ó e ń jí gìrì sí itju àwn mdé.

Ó gbà á lám̀ràn láti j́ kí ètò tó ń e agbátrù r̀ láb́ Ètò Ìrètí Ìsd̀tun má e gbàgbé àwn tó kù dí̀ káàtò fún.

Lori ètò ̀ḱ àwn mbìnrin, Báyéró s fún un pé kí ó fojú lámèyít́ wò ó kí ó lè wá nǹkan e sí i.

ba náà gbóríyin fún Olúr̀mí Tinúubú bí ó e e adúrótì fún àwn ará ìpínl̀ Plateau lásìkò gbódó-n-róṣọ tó wáyé níb̀, ó wá e é ládúrà pé kí yóò túb̀ lè e irú r̀ fún àwn aláìní yòókù.

Prev Post

Wigwe: 'I lived in deliberate denial, hoping, praying the news would be a hoax' - Amosun mourns

Next Post

Suffering under Tinubu's administration is alarming - Emir of Kano tells First Lady

Newsletter

Get every weekly update & insights

Comment(s) 0

Leave a Reply

BACK TO TOP