Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ògùn Kéde Owó Ìránwọ́ Bílíọ̀nù márùn-ún náírà láti mú Ìdẹkùn bá ọmọ Ìpínlẹ̀ náà
Home - News

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ògùn Kéde Owó Ìránwọ́ Bílíọ̀nù márùn-ún náírà láti mú Ìdẹkùn bá ọmọ Ìpínlẹ̀ náà

Feb. 15, 2024

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ògùn Kéde Owó Ìránwọ́ Bílíọ̀nù márùn-ún náírà láti mú Ìdẹkùn bá ọmọ Ìpínlẹ̀ náà

Admin By Adewale Adewale
  • 251
  • 47 min
  • 0

Ìjba ìpínl̀ Ògùn ĺj́ j́rú, ti kéde owó tí ó tó bílí̀nù márùn-ún náírà ǵǵ bí owó ìránẃ láti kojú wàhálà tó ń kojú ètò ̀r̀ ajé ní gbogbo ̀ka.

Gómìnà ìpínl̀ Ògùn, mọọba Dàp̀ Abí́dún s èyí nígbà tí ó bá ń àwn oníròyìn s̀r̀ ní ọ́fíìsì r̀ tó wà ní Òkè-Msàn ní Ab́òkúta.

Abí́dún s onírúurú ̀nà tí ìjba ti là kal̀ láti mú ìdínkù bá ìpayínkeke tí ó ń bá àwn èèyàn fínra.

Gómìnà tún àfikún r̀ pé, owó ìránẃ fún àwn aḱk̀́, owó madáńdófò lórí ètò ìlera, sísan owó àjsíl̀ owó tí wn ń y lórí owó où àwn òìṣẹ́ p̀lú pípín oúnj fún àwn aráàlú wà lára ìgbés̀ ìjba.

Ó s pé, “Àwn kò k etí ikún sí bí àwn aráàlú e ń kígbe lórí bí owó e ń gbówó lórí gegere àti bí owó náírà e ń já wál̀, ó s pé gbogbo ̀nà ni àwn ń wá láti lè mú ìnira yìí kúrò kí ìgbàyé gbádùn gbogbo mùtúmùwà lè túb̀ rú ǵǵ sí.

Ó ní, àfojúsùn àwn ni láti gbé ìgbés̀ tí yóò mú ìnira tí àwn m il̀ yìí ń kojú dínkù jj.

“Ní ̀ka ètò ̀ḱ, a óò ḱḱ ètò gb̀rún ḿwàá náírà ǵǵ bí owó ìránẃ fún àwn ǵrùn-ún ḿwàá aḱk̀́ ní gbogbo tìbútòró àwn ilé-̀ḱ alák̀́b̀r̀ àti girama ní Ìpínl̀ Ògùn.

Nígbà tí ó fún àwn aḱk̀́ tí ó j́ m ìpínl̀ yìí tí ó f́r̀ tó gb̀rún ḿtadínĺgb̀n-ó-lé-gbẹ̀ta tó kù dí̀ káàtò fún ní àwn ilé-̀ḱ Yunifásítì jákèjádò oríl̀-èdè Nàìjíríà ní owó ìránẃ gb̀rún ĺnà àád́ta náírà.

̀ka ètò ìlera, ó s di mím̀ pé, "a ó pèsè owó adíyelófò fún àwn aláboyún, mdé, àgbàlagbà, ìyàĺjà àti àwn oníe ẃ tó tó gb̀rún ĺnà ̀́d́gbẹ̀rin.

"A ó tún pèsè oúnj bí i ìrsì àti oúnj mìíràn fún àwn èèyàn tí ó tó gb̀rún ĺnà ̀́dúnrún jákèjádò ìpínl̀ Ògùn."

Ní ti àwn òìṣẹ́, ìjba yóò b̀r̀ sísán owó àjsíl̀ tí ìjba àná j wọ́n. "Fún ìdí èyí, ní báyìí, a ó máa san gb̀rún ĺnà ̀́d́gbẹ̀ta mílíọ̀nù náírà lóooù.

"Ǵǵ bí ìjba tó m ohun tó ń e, tó sì tún fi aráàlú sọ́kàn, èyí ló mú kí àpap̀ owó tí à ń f́ san báyìí j́ bílíọ̀nù márùn-ún náírà ní gbogbo ̀ka ètò ̀r̀ ajé ní Ìpínl̀ Ògùn.

“Ojúe ìjba ni láti pèsè ààbò tó dúró o re fún ̀mí àti dúkìá àwn aráàlú, Abí́dún s b́̀”.

Prev Post

Reps Urge FG to subsidise N5m 2024 hajj fare

Next Post

Single identification management system will help fight security, corruption, other vices - FG

Newsletter

Get every weekly update & insights

Comment(s) 0

Leave a Reply

BACK TO TOP